Numeri 5:23 - Yoruba Bible23 “Lẹ́yìn èyí, kí alufaa kọ ègún yìí sinu ìwé, kí ó sì fọ̀ ọ́ sinu abọ́ omi kíkorò náà. Faic an caibideilBibeli Mimọ23 Ki alufa ki o si kọ egún yi sinu iwé, ki o si fi omi kikorò na wẹ̀ ẹ nù: Faic an caibideilBíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní23 “ ‘Nígbà náà ni àlùfáà yóò kọ ègún yìí sínú ìwé kíká, yóò sì sìn ín sínú omi kíkorò náà. Faic an caibideil |