Luku 4:7 - Yoruba Bible7 Tí o bá júbà mi, tìrẹ ni gbogbo rẹ̀ yóo dà.” Faic an caibideilBibeli Mimọ7 Njẹ bi iwọ ba foribalẹ fun mi, gbogbo rẹ̀ ni yio jẹ tirẹ. Faic an caibideilBíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní7 Ǹjẹ́ bí ìwọ bá foríbalẹ̀ fún mi, gbogbo rẹ̀ ni yóò jẹ́ tìrẹ.” Faic an caibideil |
Ó ní, “Àwọn ọrọ̀ ilẹ̀ Ijipti ati àwọn ẹrù ilẹ̀ Etiopia, ati àwọn ọkunrin Seba tí wọn ṣígbọnlẹ̀, wọn óo tọ̀ ọ́ wá, wọn óo di tìrẹ, wọn óo sì máa tẹ̀lé ọ. Wọn óo wá, pẹlu ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ lẹ́sẹ̀ wọn, wọn óo sì wólẹ̀ fún ọ. Wọn óo máa bẹ̀ ọ́ pé, ‘Lọ́dọ̀ rẹ nìkan ni Ọlọrun wà, kò tún sí Ọlọrun mìíràn. Kò sí Ọlọrun mìíràn lẹ́yìn rẹ.’ ”