Numeri 16:21 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní21 “Ẹ ya ara yín sọ́tọ̀ kúrò láàrín ìjọ wọ̀nyí, kí ń ba à le pa wọ́n run lẹ́ẹ̀kan náà.” Faic an caibideilYoruba Bible21 “Ẹ bọ́ sí apá kan kí n lè rí ààyè pa àwọn eniyan náà run ní ìṣẹ́jú kan.” Faic an caibideilBibeli Mimọ21 Ẹ yà ara nyin kuro lãrin ijọ yi, ki emi ki o run wọn ni iṣéju kan. Faic an caibideil |