Numeri 12:16 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní16 Lẹ́yìn èyí, àwọn ènìyàn kúrò ní Haserotu, wọ́n sì pa ibùdó sí Aginjù Parani. Faic an caibideilYoruba Bible16 Lẹ́yìn náà, wọ́n ṣí kúrò ni Haserotu, wọ́n sì pa àgọ́ wọn sí aṣálẹ̀ Parani. Faic an caibideilBibeli Mimọ16 Lẹhin eyinì li awọn enia si ṣí kuro ni Haserotu, nwọn si dó si ijù Parani. Faic an caibideil |