Numeri 11:6 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní6 Ṣùgbọ́n báyìí gbogbo ara wa ti gbẹ, kò sí ohun mìíràn láti jẹ àfi manna nìkan tí a rí yìí!” Faic an caibideilYoruba Bible6 Ṣugbọn nisinsinyii, a kò lókun ninu mọ́, kò sí ohun tí a rí jẹ bíkòṣe mana yìí nìkan lojoojumọ.” Faic an caibideilBibeli Mimọ6 Ṣugbọn nisisiyi ọkàn wa gbẹ: kò sí ohun kan rára, bikọse manna yi niwaju wa. Faic an caibideil |