Luku 7:10 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní10 Nígbà tí àwọn oníṣẹ́ sì padà sí ilé, wọ́n bá ọmọ ọ̀dọ̀ náà tí ń ṣàìsàn, ara rẹ̀ ti dá. Faic an caibideilYoruba Bible10 Nígbà tí àwọn tí ọ̀gágun rán pada dé ilé, wọ́n rí ẹrú náà tí ara rẹ̀ ti dá. Faic an caibideilBibeli Mimọ10 Nigbati awọn onṣẹ si pada rè ile, nwọn ba ọmọ-ọdọ na ti nṣaisàn, ara rẹ̀ ti da. Faic an caibideil |