Luku 5:6 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní6 Nígbà tí wọ́n sì ti ṣe èyí, wọ́n kó ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹja: àwọ̀n wọn sì ya. Faic an caibideilYoruba Bible6 Nígbà tí ó dà á sinu omi, ẹja tí ó kó pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí àwọ̀n fẹ́ ya. Faic an caibideilBibeli Mimọ6 Nigbati nwọn si ti ṣe eyi, nwọn kó ọpọlọpọ ẹja: àwọn wọn si ya. Faic an caibideil |