Luku 24:11 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní11 Ọ̀rọ̀ wọ̀nyí sì dàbí ìsọkúsọ lójú wọn, wọn kò sì gbà wọ́n gbọ́. Faic an caibideilYoruba Bible11 Ṣugbọn bíi ìsọkúsọ ni gbogbo ọ̀rọ̀ yìí rí létí wọn. Wọn kò gba ohun tí àwọn obinrin náà sọ gbọ́. [ Faic an caibideilBibeli Mimọ11 Ọ̀rọ wọnyi si dabi isọkusọ loju wọn, nwọn kò si gbà wọn gbọ́. Faic an caibideil |