Luku 2:6 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní6 Ó sì ṣe, nígbà tí wọ́n wà níbẹ̀, ọjọ́ rẹ̀ pé tí òun yóò bí. Faic an caibideilYoruba Bible6 Ó wá yá nígbà tí wọ́n wà ní Bẹtilẹhẹmu, àkókò tó fún Maria láti bímọ. Faic an caibideilBibeli Mimọ6 O si ṣe, nigbati nwọn wà nibẹ̀, ọjọ rẹ̀ pé ti on o bí. Faic an caibideil |