Joṣua 4:1 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní1 Nígbà tí gbogbo orílẹ̀-èdè náà kọjá nínú odò Jordani tan, Olúwa sọ fún Joṣua pé, Faic an caibideilYoruba Bible1 Nígbà tí gbogbo àwọn eniyan náà rékọjá sí òdìkejì odò Jọdani tán, OLUWA wí fún Joṣua pé, Faic an caibideilBibeli Mimọ1 O si ṣe, nigbati gbogbo awọn enia rekọja Jordani tán, ni OLUWA wi fun Joṣua pe, Faic an caibideil |