Johanu 9:20 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní20 Àwọn òbí rẹ̀ dá wọn lóhùn wí pé, “Àwa mọ̀ pé ọmọ wa ni èyí, àti pé a bí i ní afọ́jú: Faic an caibideilYoruba Bible20 Àwọn òbí rẹ̀ dáhùn pé, “A mọ̀ pé ọmọ wa nìyí; ati pé afọ́jú ni a bí i. Faic an caibideilBibeli Mimọ20 Awọn obi rẹ̀ da wọn lohùn wipe, Awa mọ̀ pe ọmọ wa li eyi, ati pe a bí i li afọju: Faic an caibideil |