Johanu 9:17 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní17 Nítorí náà, wọ́n sì tún wí fún afọ́jú náà pé, “Kí ni ìwọ ní wí nípa rẹ̀, nítorí tí ó là ọ́ lójú?” Ó sì wí pé, “Wòlíì ní í ṣe.” Faic an caibideilYoruba Bible17 Wọ́n tún bi ọkunrin afọ́jú náà pé, “Kí ni ìwọ alára sọ nípa lílà tí ó là ọ́ lójú?” Ọkunrin náà ní, “Wolii ni.” Faic an caibideilBibeli Mimọ17 Nitorina nwọn si tun wi fun afọju na pe, Kini iwọ wi nitori rẹ̀, nitoriti o là ọ loju? O si wipe, Woli ni iṣe. Faic an caibideil |