Johanu 20:9 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní9 (Nítorí tí wọn kò sá à tí mọ ìwé mímọ́ pé, Jesu ní láti jíǹde kúrò nínú òkú.) Faic an caibideilYoruba Bible9 (Nítorí ohun tí Ìwé Mímọ́ wí kò tíì yé wọn pé dandan ni kí ó jí dìde ninu òkú.) Faic an caibideilBibeli Mimọ9 Nitoripe nwọn kò sá ti imọ̀ iwe-mimọ́ pe, on kò le ṣaima jinde kuro ninu okú. Faic an caibideil |