Johanu 18:6 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní6 Nítorí náà bí ó ti wí fún wọn pé, “Èmi nìyí,” wọ́n bì sẹ́yìn, wọ́n sì ṣubú lulẹ̀. Faic an caibideilYoruba Bible6 Nígbà tí ó sọ fún wọn pé, “Èmi gan-an nìyí,” wọ́n bì sẹ́yìn, ni wọ́n bá ṣubú lulẹ̀. Faic an caibideilBibeli Mimọ6 Nitorina bi o ti wi fun wọn pe, Emi niyi, nwọn bi sẹhin, nwọn si ṣubu lulẹ. Faic an caibideil |