Johanu 1:4 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní4 Nínú rẹ̀ ni ìyè wà, ìyè yìí náà sì ni ìmọ́lẹ̀ aráyé, Faic an caibideilYoruba Bible4 Òun ni orísun ìyè, ìyè náà ni ìmọ́lẹ̀ aráyé. Faic an caibideilBibeli Mimọ4 Ninu rẹ̀ ni ìye wà; ìye na si ni imọlẹ̀ araiye. Faic an caibideil |