Gẹnẹsisi 42:3 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní3 Nígbà náà ni mẹ́wàá nínú àwọn arákùnrin Josẹfu sọ̀kalẹ̀ lọ sí Ejibiti láti ra ọkà. Faic an caibideilYoruba Bible3 Àwọn arakunrin Josẹfu mẹ́wàá bá lọ sí Ijipti, wọ́n lọ ra ọkà. Faic an caibideilBibeli Mimọ3 Awọn arakunrin Josefu mẹwẹwa si sọkalẹ lọ lati rà ọkà ni Egipti. Faic an caibideil |