Gẹnẹsisi 3:4 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní4 Ejò wí fún obìnrin náà pé, “Ẹ̀yin kì yóò kú ikúkíkú kan.” Faic an caibideilYoruba Bible4 Ṣugbọn ejò náà dáhùn, ó ní, “Ẹ kò ní kú rárá, Faic an caibideilBibeli Mimọ4 Ejò na si wi fun obinrin na pe, Ẹnyin ki yio ku ikú kikú kan. Faic an caibideil |
Wọ́n dáhùn pé, “Ọkùnrin kan wá láti pàdé wa, ó sì wí fún wa pé, ‘Ẹ padà sí ọ̀dọ̀ ọba tí ó rán an yín kí ẹ sì wí fún un pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: Ṣé nítorí wí pé kò sí Ọlọ́run ní Israẹli ni o fi ń rán àwọn ènìyàn láti lọ ṣe ìwádìí lọ́wọ́ Baali-Sebubu, òrìṣà Ekroni? Nítorí náà ìwọ kò ní fi orí ibùsùn tí ìwọ dùbúlẹ̀ lé sílẹ̀. Láìsí àní àní ìwọ yóò kùú!” ’ ”