Gẹnẹsisi 15:3 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní3 Abramu sì tún tẹ̀síwájú pé, “Ìwọ kò fún mi ní ọmọ, nítorí náà ẹrú nínú ilé mi sì ni yóò jẹ́ àrólé mi.” Faic an caibideilYoruba Bible3 O kò fún mi lọ́mọ, ẹrú tí wọ́n bí ninu ilé mi ni yóo di àrólé mi!” Faic an caibideilBibeli Mimọ3 Abramu si wipe, Wo o emi ni iwọ kò fi irú-ọmọ fun: si wo o, ẹrú ti a bi ni ile mi ni yio jẹ arolé. Faic an caibideil |