Daniẹli 7:15 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní15 “Ọkàn èmi Daniẹli, dàrú, ìran tí ó wá sọ́kàn mi dẹ́rùbà mí. Faic an caibideilYoruba Bible15 “Ìran tí mo rí yìí bà mí lẹ́rù pupọ, ọkàn mi sì dààmú. Faic an caibideilBibeli Mimọ15 Ẹmi emi Danieli si rẹwẹsi ninu ara mi, iran ori mi si mu mi dãmu. Faic an caibideil |
Nígbà náà ni Daniẹli (ẹni tí à ń pè ní Belṣassari) páyà gidigidi fún ìgbà díẹ̀, èrò inú rẹ̀ sì bà á lẹ́rù. Nígbà náà ni ọba wí pé, “Belṣassari, má ṣe jẹ́ kí àlá náà tàbí ìtumọ̀ rẹ̀ kí ó dẹ́rùbà ọ́.” Belṣassari sì dáhùn wí pé, “olúwa mi, kí àlá yìí jẹ́ ti àwọn ọ̀tá a rẹ, kí ìtumọ̀ rẹ̀ sì jẹ́ ti àwọn aṣòdì sí ọ: