Online Bible

- Advertisements -




Marku 7:29 - Yoruba Bible

29 Jesu dá a lóhùn pé, “Nítorí gbolohun rẹ yìí, máa lọ sí ilé rẹ, ẹ̀mí èṣù náà ti jáde kúrò ninu ọmọ rẹ.”

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

29 O si wi fun u pe, Nitori ọ̀rọ yi, mã lọ; ẹmi ẹ̀ṣu na ti jade kuro lara ọmọbinrin rẹ.

See the chapter Copy

Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

29 “Ó sì wí fún un pé, nítorí ọ̀rọ̀ yìí, máa lọ, ẹ̀mí àìmọ́ náà ti jáde kúrò lára ọmọbìnrin rẹ.”

See the chapter Copy




Marku 7:29

Follow us:

Advertisements


Advertisements