Online Bible

- Advertisements -




Marku 7:19 - Yoruba Bible

19 Nítorí kì í wọ inú ọkàn lọ, bíkòṣe inú ikùn, a sì tún jáde.” (Báyìí ni ó pe gbogbo oúnjẹ ní mímọ́.)

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

19 Nitoriti ko lọ sinu ọkàn rẹ̀, ṣugbọn sinu ara, a si yà a jade, a si gbá gbogbo onjẹ danù?

See the chapter Copy

Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

19 Nítorí tí kò lọ sínú ọkàn rẹ̀, ṣùgbọ́n sínú ara, a sì yà á jáde, a sì gbá gbogbo oúnjẹ dànù.” (Nípa sísọ èyí, Jesu fihàn pé gbogbo oúnjẹ jẹ́ “mímọ́.”)

See the chapter Copy




Marku 7:19

Follow us:

Advertisements


Advertisements