Online Bible

- Advertisements -




Marku 3:2 - Yoruba Bible

2 Àwọn kan wà tí wọn ń ṣọ́ ọ bí yóo wo ọkunrin yìí sàn ní Ọjọ́ Ìsinmi, kí wọn lè fi í sùn.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

2 Nwọn si nṣọ ọ, bi yio mu u larada li ọjọ isimi; ki nwọn ki o le fi i sùn.

See the chapter Copy

Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

2 Àwọn kan nínú wọn sì ń wa ọ̀nà láti fi ẹ̀sùn kan Jesu, Nítorí náà, wọ́n ń ṣọ́ Ọ bí yóò mú un láradá ní ọjọ́ ìsinmi.

See the chapter Copy




Marku 3:2

Follow us:

Advertisements


Advertisements