Online Bible

- Advertisements -




Esteri 9:11 - Yoruba Bible

11 Ní ọjọ́ náà, wọ́n mú ìròyìn iye àwọn tí wọ́n pa ní Susa wá fún ọba.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

11 Li ọjọ na a mu iye awọn ti a pa ni Ṣuṣani ãfin wá siwaju ọba.

See the chapter Copy

Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

11 Ní ọjọ́ náà gan an ni a mú iye àwọn tí a pa ní ilé ìṣọ́ ti Susa wá fún ọba.

See the chapter Copy




Esteri 9:11

Follow us:

Advertisements


Advertisements