Online Bible

- Advertisements -




Esteri 7:6 - Yoruba Bible

6 Ẹsita bá dá a lóhùn pé, “Ọlọ̀tẹ̀ ati ọ̀tá náà ni Hamani eniyan burúkú yìí.” Ẹ̀rù ba Hamani gidigidi níwájú ọba ati ayaba.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

6 Esteri si wi pe, ọlọtẹ enia ati ọta na ni Hamani, ẹni buburu yi. Nigbana ni ẹ̀ru ba Hamani niwaju ọba ati ayaba.

See the chapter Copy

Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

6 Esteri sọ wí pé, “Alátakò àti ọ̀tá náà ni Hamani aláìníláárí yìí.” Nígbà náà ni Hamani wárìrì níwájú ọba àti ayaba.

See the chapter Copy




Esteri 7:6

Follow us:

Advertisements


Advertisements