Online Bible

- Advertisements -




Rutu 2:16 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

16 Bí kò ṣe pé kí ẹ mú lára àwọn ìtí sílẹ̀ fún láti ṣá, kí ẹ má sì ṣe ba a wí.”

See the chapter Copy

Yoruba Bible

16 Kí ẹ tilẹ̀ fa ọkà yọ fún un ninu ìtí, kí ẹ sì tún fi í sílẹ̀ láti ṣa ọkà, ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ yọ ọ́ lẹ́nu.”

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

16 Ki ẹ si yọ diẹ ninu ití fun u, ki ẹ si fi i silẹ, ki ẹ si jẹ ki o ṣà a, ẹ má si ṣe bá a wi.

See the chapter Copy




Rutu 2:16

Follow us:

Advertisements


Advertisements