Online Bible

- Advertisements -




Rutu 1:3 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

3 Ní àsìkò tí wọ́n ń gbé ibẹ̀, Elimeleki, ọkọ Naomi kú, ó sì ku òun pẹ̀lú àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin méjèèjì.

See the chapter Copy

Yoruba Bible

3 Nígbà tí ó yá, Elimeleki kú, ó bá ku Naomi, opó rẹ̀, ati àwọn ọmọkunrin rẹ̀ mejeeji.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

3 Elimeleki ọkọ Naomi si kú; o si kù on, ati awọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin mejeji.

See the chapter Copy




Rutu 1:3

Follow us:

Advertisements


Advertisements