Online Bible

- Advertisements -




Numeri 2:25 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

25 Ní ìhà àríwá: ni ìpín Dani yóò pa ibùdó sí lábẹ́ ọ̀págun wọn. Olórí Dani ni Ahieseri ọmọ Ammiṣaddai.

See the chapter Copy

Yoruba Bible

25 Àsíá ibùdó ẹ̀yà Dani yóo wà ní ìhà àríwá ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí; Ahieseri, ọmọ Amiṣadai, ni yóo jẹ́ olórí wọn.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

25 Ọpagun ibudó Dani ni ki o wà ni ìha ariwa gẹgẹ bi ogun wọn: Ahieseri ọmọ Ammiṣaddai yio si jẹ́ olori awọn ọmọ Dani.

See the chapter Copy




Numeri 2:25

Follow us:

Advertisements


Advertisements