Online Bible

- Advertisements -




Numeri 1:16 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

16 Àwọn wọ̀nyí ni wọ́n yàn nínú àwùjọ ènìyàn, olórí àwọn ẹ̀yà baba wọn. Àwọn ni olórí àwọn ẹbí Israẹli.

See the chapter Copy

Yoruba Bible

16 Àwọn ni olórí tí a yàn ninu àwọn ọmọ Israẹli, olukuluku wọn jẹ́ olórí ninu ẹ̀yà wọn, ati ní ìdílé wọn.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

16 Wọnyi li awọn ti a yàn ninu ijọ, olori ẹ̀ya awọn baba wọn, awọn olori ẹgbẹgbẹrun ni Israeli.

See the chapter Copy




Numeri 1:16

Follow us:

Advertisements


Advertisements