Online Bible

- Advertisements -




Marku 7:29 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

29 “Ó sì wí fún un pé, nítorí ọ̀rọ̀ yìí, máa lọ, ẹ̀mí àìmọ́ náà ti jáde kúrò lára ọmọbìnrin rẹ.”

See the chapter Copy

Yoruba Bible

29 Jesu dá a lóhùn pé, “Nítorí gbolohun rẹ yìí, máa lọ sí ilé rẹ, ẹ̀mí èṣù náà ti jáde kúrò ninu ọmọ rẹ.”

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

29 O si wi fun u pe, Nitori ọ̀rọ yi, mã lọ; ẹmi ẹ̀ṣu na ti jade kuro lara ọmọbinrin rẹ.

See the chapter Copy




Marku 7:29

Follow us:

Advertisements


Advertisements