Online Bible

- Advertisements -




Marku 6:51 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

51 Nígbà náà ni ó gòkè sínú ọkọ̀ pẹ̀lú wọn, ìjì líle náà sì dáwọ́ dúró. Ẹ̀rù sì bà wọ́n rékọjá gidigidi, ẹnu sì yà wọ́n.

See the chapter Copy

Yoruba Bible

51 Ó bá wọ inú ọkọ̀ tọ̀ wọ́n lọ, afẹ́fẹ́ bá rọlẹ̀. Ẹnu yà wọ́n lọpọlọpọ,

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

51 O si wọ̀ inu ọkọ̀ tọ̀ wọn lọ; afẹfẹ si da: ẹ̀ru si ba wọn rekọja gidigidi ninu ara wọn, ẹnu si yà wọn.

See the chapter Copy




Marku 6:51

Follow us:

Advertisements


Advertisements