Online Bible

- Advertisements -




Marku 1:22 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

22 Ẹnu sì ya ìjọ ènìyàn nítorí ìkọ́ni rẹ̀, nítorí pé ó ń kọ́ni bí ẹni tí ó ní àṣẹ, kì í ṣe bí àwọn olùkọ́ òfin ṣe ń kọ́ àwọn ènìyàn.

See the chapter Copy

Yoruba Bible

22 Ẹnu ya àwọn tí ó gbọ́ ẹ̀kọ́ rẹ̀, nítorí ó ń kọ́ wọn bí ẹni tí ó ní àṣẹ, yàtọ̀ sí bí àwọn amòfin ṣe ń kọ́ wọn.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

22 Ẹnu si yà wọn si ẹkọ́ rẹ̀: nitoriti o nkọ́ wọn bi ẹniti o li aṣẹ, kì isi ṣe bí awọn akọwe.

See the chapter Copy




Marku 1:22

Follow us:

Advertisements


Advertisements