Luku 1:2 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní2 àní gẹ́gẹ́ bí àwọn ìránṣẹ́ ọ̀rọ̀ náà, tí ó ṣe ojú wọn láti ìbẹ̀rẹ̀ ti fi lé wa lọ́wọ́. See the chapterYoruba Bible2 àwọn tí nǹkan wọnyi ṣojú wọn, tí wọ́n sì sọ fún wa. See the chapterBibeli Mimọ2 Ani gẹgẹ bi awọn ti o ṣe oju wọn lati ibẹrẹ, ti nwọn si jasi iranṣẹ ọrọ na, ti fi le wa lọwọ; See the chapter |