Online Bible

- Advertisements -




Johanu 2:8 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

8 Lẹ́yìn náà ni ó wí fún wọn pé, “Ẹ bù jáde lára rẹ̀ kí ẹ sì gbé e tọ alábojútó àsè lọ.” Wọ́n sì gbé e lọ;

See the chapter Copy

Yoruba Bible

8 Ó bá tún wí fún wọn pé, “Ẹ bù ninu rẹ̀ lọ fún alága àsè.” Wọ́n bá bù ú lọ.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

8 O si wi fun wọn pe, Ẹ bù u jade nisisiyi, ki ẹ si gbé e tọ̀ olori àse lọ. Nwọn si gbé e lọ.

See the chapter Copy




Johanu 2:8

Follow us:

Advertisements


Advertisements