Online Bible

- Advertisements -




Johanu 2:20 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

20 Nígbà náà ní àwọn Júù wí pé, “Ọdún mẹ́rìn-dínláàádọ́ta ni a fi kọ́ tẹmpili yìí, ìwọ ó ha sì tún un kọ ní ọjọ́ mẹ́ta?”

See the chapter Copy

Yoruba Bible

20 Àwọn Juu wí fún un pé, “Aadọta ọdún ó dín mẹrin ni ó gbà wá láti kọ́ Tẹmpili yìí, ìwọ yóo wá kọ́ ọ ní ọjọ́ mẹta?”

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

20 Nigbana li awọn Ju wipe, Ọdún mẹrindiladọta li a fi kọ́ tẹmpili yi, iwọ o ha si gbé e ró ni ijọ mẹta?

See the chapter Copy




Johanu 2:20

Follow us:

Advertisements


Advertisements