Online Bible

- Advertisements -




Esteri 9:11 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

11 Ní ọjọ́ náà gan an ni a mú iye àwọn tí a pa ní ilé ìṣọ́ ti Susa wá fún ọba.

See the chapter Copy

Yoruba Bible

11 Ní ọjọ́ náà, wọ́n mú ìròyìn iye àwọn tí wọ́n pa ní Susa wá fún ọba.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

11 Li ọjọ na a mu iye awọn ti a pa ni Ṣuṣani ãfin wá siwaju ọba.

See the chapter Copy




Esteri 9:11

Follow us:

Advertisements


Advertisements