Online Bible

- Advertisements -




Esteri 7:10 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

10 Wọ́n sì so Hamani sórí igi tí ó ti pèsè sílẹ̀ fún Mordekai, ìbínú ọba sì rọ̀.

See the chapter Copy

Yoruba Bible

10 Ọba bá ní kí wọ́n lọ gbé Hamani kọ́ sí orí rẹ̀. Wọ́n bá gbé Hamani kọ́ sí orí igi tí ó ti rì mọ́lẹ̀ fún Modekai, nígbà náà ni inú ọba tó rọ̀.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

10 Bẹ̃ni nwọn so Hamani rọ̀ sori igi ti o ti rì fun Mordekai; ibinu ọba si rọ̀.

See the chapter Copy




Esteri 7:10

Follow us:

Advertisements


Advertisements