Online Bible

- Advertisements -




Esteri 6:14 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

14 Bí wọ́n ṣe ń bá a sọ̀rọ̀, àwọn ìwẹ̀fà ọba wọlé, wọ́n sì kán Hamani lójú láti lọ sí ibi àsè tí Esteri ti pèsè.

See the chapter Copy

Yoruba Bible

14 Bí wọ́n ti ń bá Hamani sọ̀rọ̀ lọ́wọ́ ni àwọn ìwẹ̀fà ọba dé láti yára mú un lọ sí ibi àsè Ẹsita.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

14 Bi nwọn si ti mba a sọ̀rọ lọwọ, awọn ìwẹfa ọba de, lati wá mu Hamani yára wá si ibi àse ti Esteri sè.

See the chapter Copy




Esteri 6:14

Follow us:

Advertisements


Advertisements