Online Bible

- Advertisements -




Esteri 3:11 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

11 Ọba sọ fún Hamani pé, “pa owó náà mọ́, kí o sì ṣe ohun tí ó wù ọ́ fún àwọn ènìyàn náà.”

See the chapter Copy

Yoruba Bible

11 Ọba sọ fún un pé, “Má wulẹ̀ san owó kankan, àwọn eniyan náà wà ní ìkáwọ́ rẹ, lọ ṣe wọ́n bí o bá ti fẹ́.”

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

11 Ọba si wi fun Hamani pe, a fi fadaka na bùn ọ, ati awọn enia na pẹlu, lati fi wọn ṣe bi o ti dara loju rẹ.

See the chapter Copy




Esteri 3:11

Follow us:

Advertisements


Advertisements