Online Bible

- Advertisements -




Eksodu 7:5 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

5 Àwọn ará Ejibiti yóò sì mọ̀ pé Èmi ni Olúwa ní ìgbà tí mo bá na ọwọ́ mi jáde lé Ejibiti, tí mo sì mú àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò níbẹ̀.”

See the chapter Copy

Yoruba Bible

5 Àwọn ará Ijipti yóo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA, nígbà tí mo bá nawọ́ ìyà sí Ijipti tí mo sì kó àwọn eniyan Israẹli jáde kúrò láàrin wọn.”

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

5 Awọn ara Egipti yio si mọ̀ pe, emi li OLUWA, nigbati mo ba nà ọwọ́ mi lé Egipti, ti mo si mú awọn ọmọ Israeli jade kuro lãrin wọn.

See the chapter Copy




Eksodu 7:5

Follow us:

Advertisements


Advertisements