Online Bible

- Advertisements -




Eksodu 7:24 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

24 Nígbà náà ni gbogbo àwọn ará Ejibiti bẹ̀rẹ̀ sí í gbẹ́ etí odò Naili láti wá omi tí wọn yóò mu, nítorí wọn kò le è mu omi tí ó wà nínú odò náà.

See the chapter Copy

Yoruba Bible

24 Gbogbo àwọn ará Ijipti bẹ̀rẹ̀ sí gbẹ́lẹ̀ káàkiri yíká odò Naili, pé bóyá wọn á jẹ́ rí omi mímu nítorí pé wọn kò lè mu omi odò Naili mọ́.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

24 Gbogbo awọn ara Egipti si wàlẹ yi odò na ká fun omi mimu; nitoriti nwọn kò le mu ninu omi na.

See the chapter Copy




Eksodu 7:24

Follow us:

Advertisements


Advertisements