Online Bible

- Advertisements -




Eksodu 7:18 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

18 Àwọn ẹja tí ó wà nínú odò Naili yóò kú, odò náà yóò sì máa rùn, àwọn ará Ejibiti kò sì ni lè mu omi rẹ̀.’ ”

See the chapter Copy

Yoruba Bible

18 Gbogbo ẹja inú odò náà yóo kú, odò náà yóo sì máa rùn, tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn ará Ijipti kò ní lè mu omi inú rẹ̀ mọ́.’ ”

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

18 Ẹja ti o wà ninu odò na yio si kú, odò na yio si ma rùn; awọn ara Egipti yio si korira ati ma mu ninu omi odò na.

See the chapter Copy




Eksodu 7:18

Follow us:

Advertisements


Advertisements