Online Bible

- Advertisements -




Eksodu 6:26 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

26 Aaroni àti Mose yìí kan náà ni Olúwa sọ fún pé, “Ẹ kó àwọn ará Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti ní ìsọ̀rí ìsọ̀rí.”

See the chapter Copy

Yoruba Bible

26 Aaroni ati Mose ni OLUWA pè, tí ó sì wí fún pé kí wọ́n kó àwọn eniyan Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

26 Wọnyi ni Aaroni on Mose na, ẹniti OLUWA sọ fun pe, Ẹ mú awọn ọmọ Israeli jade kuro ni ilẹ Egipti, gẹgẹ bi ogun wọn.

See the chapter Copy




Eksodu 6:26

Follow us:

Advertisements


Advertisements