Online Bible

- Advertisements -




Eksodu 5:17 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

17 Farao sí dáhùn wí pé, “Ọ̀lẹ ni yín, ọ̀lẹ! Èyí ni ó mú kí ẹ̀yin máa sọ ní ìgbà gbogbo pé, ‘Ẹ jẹ́ kí a lọ, kí a sì rú ẹbọ sí Olúwa.’

See the chapter Copy

Yoruba Bible

17 Ṣugbọn Farao dá wọn lóhùn pé, “Ọ̀lẹ ni yín, ẹ kò fẹ́ ṣiṣẹ́ ni ẹ fi ń sọ pé kí n jẹ́ kí ẹ lọ rúbọ sí OLUWA.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

17 Ṣugbọn on wipe, Ẹnyin ọlẹ, ẹnyin ọlẹ: nitorina li ẹ ṣe wipe, Jẹ ki a lọ ṣẹbọ si OLUWA.

See the chapter Copy




Eksodu 5:17

Follow us:

Advertisements


Advertisements