Online Bible

- Advertisements -




Eksodu 4:26 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

26 Nítorí náà Olúwa yọ̀ǹda rẹ láti ìgbà tí ó ti wí pé, “Ẹlẹ́jẹ̀ ni ìwọ í ṣe.” Èyí tó túmọ̀ sí ìkọlà abẹ́.

See the chapter Copy

Yoruba Bible

26 OLUWA bá fi Mose sílẹ̀, kò pa á mọ́. Nítorí àṣà ilà abẹ́ kíkọ náà ni Sipora ṣe wí pé, ọkọ tí ọ̀rọ̀ rẹ̀ gba kí á ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀ ni Mose.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

26 Bẹ̃li o jọwọ rẹ̀ lọwọ lọ. Nigbana ni Sippora wipe, Ọkọ ẹlẹjẹ ni iwọ nitori ikọlà na.

See the chapter Copy




Eksodu 4:26

Follow us:

Advertisements


Advertisements