Online Bible

- Advertisements -




Eksodu 4:19 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

19 Nísinsin yìí, Olúwa ti sọ fún Mose ni ilẹ̀ Midiani pé, “Máa padà lọ sí Ejibiti, nítorí àwọn ti ó fẹ́ pa ọ ti kú.”

See the chapter Copy

Yoruba Bible

19 OLUWA sọ fún Mose ní Midiani pé, “Pada lọ sí Ijipti, nítorí pé gbogbo àwọn tí wọn ń lépa ẹ̀mí rẹ ti kú tán.”

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

19 OLUWA si wi fun Mose ni Midiani pe, Lọ, pada si Egipti: nitori gbogbo enia ti nwá ẹmi rẹ ti kú tán.

See the chapter Copy




Eksodu 4:19

Follow us:

Advertisements


Advertisements