Online Bible

- Advertisements -




Eksodu 3:2 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

2 Níbẹ̀ ni angẹli Olúwa ti yọ sí i nínú ọ̀wọ́-iná tí ń jó láàrín igbó. Mose rí i pé iná ń jó nínú igbó ṣùgbọ́n igbó kò run

See the chapter Copy

Yoruba Bible

2 Angẹli OLUWA farahàn án ninu ahọ́n iná láàrin ìgbẹ́; bí ó ti wò ó, ó rí i pé iná ń jó nítòótọ́, ṣugbọn igbó náà kò jóná.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

2 Angeli OLUWA si farahàn a ninu ọwọ́ iná lati inu ãrin igbẹ̀: on si wò, si kiyesi i, iná njó igbẹ́, igbẹ́ na kò si run.

See the chapter Copy




Eksodu 3:2

Follow us:

Advertisements


Advertisements