Online Bible

- Advertisements -




Eksodu 3:10 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

10 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, lọ, Èmi yóò rán ọ sí Farao láti kó àwọn ènìyàn Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti.”

See the chapter Copy

Yoruba Bible

10 Wá, n óo rán ọ sí Farao, kí o lè lọ kó àwọn eniyan mi, àwọn ọmọ Israẹli, jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti.”

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

10 Nitorina wá nisisiyi, emi o si rán ọ si Farao, ki iwọ ki o le mú awọn enia mi, awọn ọmọ Israeli, lati Egipti jade wá.

See the chapter Copy




Eksodu 3:10

Follow us:

Advertisements


Advertisements