Online Bible

- Advertisements -




Eksodu 2:18 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

18 Nígbà ti àwọn ọmọbìnrin náà padà dé ọ̀dọ̀ Reueli baba wọn, ó béèrè lọ́wọ́ wọn pé “Èéṣe tí ẹ̀yin fi tètè dé ni òní?”

See the chapter Copy

Yoruba Bible

18 Nígbà tí wọ́n pada dé ọ̀dọ̀ Reueli, baba wọn, ó bi wọ́n pé, “Ó ṣe ya yín tó báyìí lónìí?”

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

18 Nigbati nwọn si padà dé lati ọdọ Reueli baba wọn, o ni Ẽtiri ti ẹnyin fi tète dé bẹ̃ loni?

See the chapter Copy




Eksodu 2:18

Follow us:

Advertisements


Advertisements