Online Bible

- Advertisements -




Daniẹli 6:11 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

11 Nígbà náà ni, àwọn ọlọ̀tẹ̀ yìí kó ara wọn jọ, wọ́n sì rí Daniẹli tí ó ń gba àdúrà, ó sì ń bẹ̀bẹ̀ fún àánú lọ́dọ̀ Ọlọ́run.

See the chapter Copy

Yoruba Bible

11 Àwọn ọkunrin wọnyi bá kó ara wọn jọ. Wọ́n wá wo Daniẹli níbi tí ó ti ń gbadura, tí ó sì ń bẹ̀bẹ̀ níwájú Ọlọrun rẹ̀.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

11 Nigbana ni awọn ọkunrin wọnyi rìn wọle, nwọn si ri Danieli ngbadura, o si mbẹbẹ niwaju Ọlọrun rẹ̀.

See the chapter Copy




Daniẹli 6:11

Follow us:

Advertisements


Advertisements