Online Bible

- Advertisements -




Daniẹli 3:21 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

21 Nígbà náà ni a dè wọ́n pẹ̀lú àwọ̀tẹ́lẹ̀ wọn, ṣòkòtò, ìbòrí àti àwọn aṣọ mìíràn, a sì jù wọ́n sínú iná ìléru.

See the chapter Copy

Yoruba Bible

21 Wọ́n di àwọn mẹtẹẹta pẹlu agbádá, ati aṣọ àwọ̀tẹ́lẹ̀, ati fìlà wọn, ati àwọn aṣọ wọn mìíràn, wọ́n sì sọ wọ́n sí ààrin adágún iná tí ń jó.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

21 Nigbana ni a dè awọn ọkunrin wọnyi ti awọn ti agbáda, ṣokoto, ati ibori wọn, ati ẹwu wọn miran, a si gbé wọn sọ si ãrin iná ileru ti njo.

See the chapter Copy




Daniẹli 3:21

Follow us:

Advertisements


Advertisements